Business

N I G E R I A

Africa In Miniature

World News in Yoruba


From The BBC

Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ondo tẹ babaláwo àtàwọn tó ń fi ẹ̀yà ara èèyàn gún ọṣẹ
Lasiko to n awọn akọroyin sọrọ, babalawo Quadri Lawal sọ pe wọn ma n lo eya ara awọn eniyan lati fi gun ọsẹ fun awọn to ba nilo rẹ, to si jẹ pe eya ara ti awọn onibara wọn ba bere fun lawọn ma n wa kiri.


Ṣé lóòtọ́ọ́ ni ìjọba ìpínlẹ̀ Eko dá àwọn olùgbé ìlú Eko kan padà sí ìpínlẹ̀ wọn l'Osun?
Iroyin naa to lu ori ayelujara pa sọ pe ni ṣe lawọn ọlọpaa sa awọn ọdọ kaakiri lawọn oju popo kan niluu Eko ti wọn si fi ọkọ akero nla ko wọn pada si ipinlẹ Osun.


Àgbàrá òjò gbé ọgọ́fà èèyàn lọ
Ajọ to n ri si ọrọ oju ọjọ ni Brazil jẹ ko di mimọ pe ko si nnkan meji to fa agbara yii to kọja ojo arọọrọda to rọ lọ.


Ìjọba fáwọn olùgbé ilé àkọ́patì Ikoyi Tower l'Eko lọ́jọ́ méjì láti kúrò níbẹ̀, bí bẹ́ẹ̀ kọ̀ọ́...
Kọmiṣọna fọrọ eto ayika ati ọrọ omi nipinlẹ naa, Tokunbọ Wahab lo sọ eyi di mimọ lasiko to ṣe abẹwo si agbegbe naa, nibi ti awọn eeyan n sun si lai gba aṣẹ.


Wo bí àṣírí ọ̀gá bánkì tó rí ẹ̀wọn ọdún mọ́kànlélọ́gọ́fà he lórí ẹ̀sùn jìbìtì N112m ṣe tú
Adajọ S. N. Odili gbe idajọ naa kalẹ lẹyin to ni awọn ẹri toun ri gba lori ẹsun ti wọn fi kan Placidus kọja ohun ti wọn le dawọ bo mọlẹ.


Akẹ́kọ̀ọ́ Kwara méjì fakọyọ nínú ìdánwò JAMB, gba máàkì 358 àti 362
Akekọọ ile ẹkọ girama ipinlẹ Kwara wa lara awọn akẹkọọ to fakọyọ julọ ninu idanwo JAMB ọdun 2024.


Àwọn ọ̀dọ́ bẹ̀rẹ̀ ìfẹ̀hónúhàn l’Osun lórí ọ̀wọ́ngógó epo, iná mọ̀nàmọ́ná àti oúnjẹ
Iwọde naa lo waye niluu Osogbo nipinlẹ Osun.


Ẹnikẹ́ni tó bá ṣe owó náírà ní ìṣekúṣe lọ́wọ́ yìí yóò fojú winá òfin – Mínísítà ètò ìròyìn
Minisita eto iroyin sọ pe naira jẹ iṣura ''orilẹede wa, nitori naa, ko si ẹni to maa ri bi wọn ṣe n tẹ iṣura mọlẹ ti inu rẹ maa dun.’’


Adájọ́ àgbà ìpínlẹ̀ Ogun dá ẹlẹ́wọ̀n mẹ́ta sílẹ̀, ó ní kí wọ́n má d'ẹ́ṣẹ̀ mọ́
Onidajọ Mosunmọla Dipẹolu paṣẹ yii lasiko abẹwo rẹ si ọgba ẹwọn to wa niluu Ilaro, ijọba ibilẹ Guusu Yewa.


Afurasí ìbejì tó n jalè dèrò àtìmọ́lé l’Ekiti
Ninu atẹjade ti ọga ọlọpaa Ekiti, Adeniran Akinwale gbe jade, eyi ti Sunday Abutu to jẹ agbẹnusọ buwọ lu laipẹ yii lo ti jẹ ko di mimọ pe ilu Ado-Ekiti lọwọ ti tẹ awọn mẹrẹẹrin.


Àjọ EFCC mú ẹ̀rí tuntun lọ sílẹ̀ ẹjọ́ lórí ọ̀rọ̀ Emefiele
Rotimi Oyedepo to jẹ agbẹjọro EFCC ni awọn ẹri naa ni awọn gba lati ọdọ amugbalẹgbẹ Godwin Emefiele tẹlẹ, ṣaaju asiko ti yoo yọju siwaju ile-ẹjọ lati sọ tẹnu rẹ.


Ìjọba Nàíjíríà sọ̀rọ̀ lórí ikú Daniel Anjọrin ọmọ ọdún mẹ́rìnlá tí wọ́n gún pa ní London
Yatọ si eyi, Hainault tun wa lara awọn agbegbe ti awọn eeyan n wa julọ lori ikanni ayelujara ti Google lasiko yii.


Ìjà parí! Ogogo àti Yinka Quadri dìmọ́ ara wọn lẹ́yìn tí Ajobiewe báwọn dá si
Ṣáájú ni àwọn ìròyìn kan ti ń lọ lórí ayélujára pé nǹkan kò lọ déédé láàárín àwọn àgbà òṣèré méjéèjì láti ọdún tó kọjá àmọ́ ọ̀pọ̀ ènìyàn ni kò gbàgbọ́.


Ìjì líle gba ẹ̀mí èèyàn mẹ́wàá, àwọn 20 di àwátì
Afẹfẹ iji lile naa lo fa agbara ojo nla, eyi to ṣakoba fun iku awọn eeyan naa, ati bi awọn ogun tun ṣe poora.


Kí ló fa aáwọ̀ tó jẹ́ káwọn afurasí jàndùkú dáná sun ọjà Ile-Epo l'Eko?
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti kede pe awọn ti fọwọ ṣinkun ofin mu aadọta afurasi janduku ti wọn dana sun ọja Ile-Epo lagbegbe Abule Egba nipinlẹ Eko ni Ọjọbọ ọjọ keji oṣu Karun ọdun 2024 yii.


Ọmọọba Harry àti Meghan Markle fẹ́ ṣàbẹ̀wò sí Naijiria l’oṣu karun-un
Invictus Games ni idije ere idaraya ti wọn ṣagbekalẹ rẹ fawọn oṣiṣẹ ologun ati agbofinro ti wọn farapa loju ogun, lati maa fi dun wọn ninu.


Israel/Gaza: Ẹ jọ̀wọ́ ogun sílẹ̀ kí ọmọ mi le wálé
Iya Hersh ni ibanujẹ lo jẹ nigba ti oun ri fọnran naa.


A ti mú Ibrahim Abdullahi tó wà nídi ìkọlù sí èrò inú reluwé Kaduna sí Abuja- Ọlọ́pàá
Olumuyiwa Adejọbi sọ pe Ibrahim Abdullahi lorukọ ọkunrin naa, ati pe Mande ni inagijẹ ti ọpọ awọn eeyan mọ ọn si.


A ti mọ ọlọ́pàá tó yìnbọn pa Toheeb Eniafe ní ilé-epo ní Eko- Ọlọ́pàá
Ṣugbọn sibẹ, agbẹnusọ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Benjamin Hundeyin ti fidi rẹ mulẹ pe ọlọpaa ni ẹni naa, ati pe Special Protection Unit (SPU) Base 17 to wa ni Lion Building l’Eko lo ti n ṣiṣẹ.


Agbẹjọ́rò wọ́ Adelabu àtàwọn míì lọ sílé ẹjọ́ fẹ́sùn pínpín iná mọ̀nàmọ́ná sí ìsọ́rí
Àwọn mìíràn tí Akingbolu tún pé lẹ́jọ́ ni àjọ tó ń rí sí ọ̀rọ̀ iná mọ̀nàmọ́ná Nàìjíríà, Nigeria Electricity Regulatory Commission (NERC) àti Ikeja Electricity Distribution Company (IKEDC).


Ojú mi ri tó lẹ́yìn tí ìyàwó mi jáde láyé ní ọjọ́ kẹta tó bí ìbẹta- Gafar
Gafar ní ìdùnnú àwọn tún lékún nígbà tí àwọn lọ ṣe àyẹ̀wò, tí wọ́n sì sọ fún àwọn pé ìbejì ló wà nínú ìyàwó òun.


Wọ́n fẹ̀sùn kan Israel pé wọ́n ń pète ogun nípa ìṣekúpa ọmọdé
Ninu iwadi sini ikọ ologun Israel ni West Bank, BBC ṣe afihan ohun to waye lọjọ ti awọn ọmọdekunrin meji naa ku.


Ìjọba Nàíjíríà sọ̀rọ̀ lórí ikú Daniel Anjọrin ọmọ ọdún mẹ́rìnlá tí wọ́n gún pa ní London
Yatọ si eyi, Hainault tun wa lara awọn agbegbe ti awọn eeyan n wa julọ lori ikanni ayelujara ti Google lasiko yii.


Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko tún ṣàwárí abẹ́ afárá ni Osborne ní Island tí àwọn èèyàn n gbé
Tokunbọ Wahab ni abẹ afara Osborne to wa ni Ikoyi lawọn ti ṣawari ibi ti awọn eeyan naa sọ di ile wọn lati maa gbe.


Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ fún ìjọba di ìparí oṣù yìí láti san N615,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jùlọ tí wọ́n ń bèèrè
Gomina ipinle Eko, Babajide Sanwo-Olu ti sọ pe ijọba oun ṣetan lati san owo oṣiṣẹ to kere julọ ti ijọba apapọ ba kede.


Kò sí nǹkan tó máa dá ìkọlù wa sí Rafah dúró - Netanyahu
Eyi lo jade lasiko ti igbinyanju pe ki adehun waye pe ki awọn juwọ ogun silẹ, ti wọn si tu awọn eeyan to wa ni ahamọ silẹ.


Àwọn afurasí ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn pa èèyàn kan, jó ilé ìgbé méjì gbúrúgbúrú ní Kwara
Iroyin ni lalẹ ọjọ Aje, ọjọ Kọkandinlọgbọn, oṣu Kẹrin, ọdun 2024 ni rogbodiyan bẹ silẹ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa ti wọn si faa titi di ọjọ Iṣẹgun.


“Lẹ́yìn ọdún kan tí wọ́n fi ipá bá ọmọ mi ọmọ odún mẹ́ta lòpọ̀, mò ń wá ìdájọ́ òdodo”
“Nnkan to ṣẹlẹ si ọmọ mi, mi o fẹ ko ṣẹlẹ si ọmọ ẹlomiran.”


Òjò ńlá àti omíyalé ṣekúpa èèyàn tó lé ní 40
Ojo arọrọda to lagbara lo fa iṣẹlẹ naa, ti o si tun sọ ọpọlọpọ eeyan di alai ni ile lori lẹyin ti Damu to wa ni Kamuchiri ni iwọ oorun Kenya ya.


Ọjọ́ àwọn òṣìṣẹ́ lágbàáyé: Ìdí tí wọ́n fi yan ọjọ́ àkọ́kọ́ oṣù Karùn-ún?
Lẹyin ti Ogun Agbaye akọkọ pari, ti ayipada rere ti n ba awọn oṣiṣẹ, ti idagbasoke ti n de pẹlu iyanju awọn ajafẹtọọ ọmọniyan ni Russia, o dohun ti awọn oṣiṣẹ n beere ohun gbogbo to tọ si wọn kaakiri aye.


Sola Sobowale ṣàlàyé bí ó ṣe rìn ìrìnàjo láti ayé 'Toyin Tomato' lọ ṣé 'Caregiver' ni London
Ilumọka oṣere, ẹni ọdun mejidinlọgọta tan imọlẹ si awọn iṣẹlẹ yii lasiko to n ṣe ifọrọwerọ lori eto Teju Baby Face lọjọ Isẹgun.


Iléeṣẹ́ O Pay ti dá a padà fún CBN, wọ́n si bá àwon Oníbàárà wọn sọ̀rọ̀ pé...
Àwọn ilé iṣẹ́ bíi Opay, Kuda Bank, Palmpay àti Moniepoint ni ọ̀rọ̀ náà kàn, tí wọn kò ní ní àǹfàní láti gba àwọn oníbàárà tuntun láàyè láti ṣí akoto owó pẹ̀lú wọn fún ìgbà kan ná.


A ó fòfin dé 'Loan App' tó bá ń dún kookò mọ́ àwọn onîbàárà wọn- FCCPC
Ọga fun ileeṣẹ ijọba, Federal Competitiona & Consumer Protection Commission, FCCPC ni idunkoko yoo di ohun igbagbe laipẹ.


Kí ló fa gbas-gbos láàrin Davido àti Wizkid lórí ayélujára?
Ori itakun ayelujara X ni rogbodiyan naa ti waye lopin ọsẹ.


Wo ohun tí àwọn aráàlú ń là kọjá nítorí àìrí epo bẹntiróòlù rà lónìí
Bo tilẹ jẹ pe ajọ NNPCL to n ri si ọrọ epo rọbi sọ lopin ọsẹ wi pe awọn ni epo to to ọmọ Naijiria lo ni ipamọ, alukoro ẹgbẹ IPMAN, Ọgbẹni Chinedu Ukadike ti fidi rẹ mulẹ pe ko si epo to to araalu lo ni Naijiria lọwọ yii.


Wo àwọn nǹkan méje tí o kò mọ̀ nípa Egbin Orun, akọrin ẹ̀mí tó dolóògbé
Olorin ẹmi bii tiẹ, Esther Igbẹkẹle, lo fi iroyin iku naa soju opo Instagram rẹ lọjọ Satide, ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹrin yii.


'Ìbejì ni wá ṣùgbọ́n àyẹ̀wò DNA ní bàbá ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ló bí wa'
Awọn onimọ sayensi ṣalaye pe, iru iṣẹlẹ yii ṣọwọn, ti ko si ju mẹwa lọ to ni akọsilẹ lagbaye ṣugbọn o wọpọ laarin ẹranko.


Oyún oṣù méje ààbọ̀, tí Dókítà gbé jáde nínú ìyá rẹ̀ ní Gaza, ti jáde láyé
Ẹlẹmi gba ẹmi ọmọ jojolo naa ni Ọjọbọ ana, ti wọn si ti sin i si ẹgbẹ iya rẹ ẹni ti wọn fi orukọ rẹ sọ ọ.


Ìwọ́de gbòde ní Australia láti fòpin sí pípa àwọn obìnrin lọ́nà àìtọ́
Olóòtú ìjọba Australia, Anthony Albanese ní ọ̀rọ̀ náà ti di ohun tó ń dààmú gbogbo orílẹ̀ èdè àwọn.


Kí ló dé tí àwọn èèyàn kan ń fi apá jánú lórí ètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ Ọ̀yọ́?
Ẹwẹ, ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) n'ipinlẹ Ọyọ ti fi ọrọ lede wi pe irọ lasan ni pe eto idibo naa lọ ni irọwọrọsẹ,


Mọ̀ nípa ẹgbẹ́ kan tó wà fún àwọn obìnrin tí kò fẹ́ l'ọ́mọ láyé
Ileeṣẹ BBC ba awọn obinrin to jẹ ọmọ ẹgbẹ Bristol Childfree Women sọrọ, wọn si salaye idi ti wọn ri ti wọn fi pinnu igbesẹ yii.


Wo pàtàkì iṣan tó ń ṣiṣẹ́ bíi ọkàn, mú kí èèyàn fẹsẹ̀ méjì rìn, ó tún ń mú kí ẹ̀jẹ̀ ṣàn lára
Dokita Carles Pedret, akọṣẹmọṣẹ lati ileewe to n ri si ilera nipa ere idaraya ni Yunifasiti Barcelona ni iṣan Soleus nilo lati maa ṣiṣẹ deede keeyan le wa lalaafia ara.


One Step At A Time

This old adage, more relevant than ever



Our Objective

  • Support and encourage current members as and when the need arises fairly and honestly
  • Grow our membership by reaching out through formal and informal social gatherings
  • Extend charitable assistance to the needy and wanting
  • Promote and maintain friendship, members and other colleagues who are non members of Soyuznikis-UK
  • Promote the group locally and worldwide
Our Mission
Soyuznikis-UK is a union for Nigerians who have studied in the former Union of Soviets Socialist Republic (USSR). Soyuznikis comes from the Russian word ‘Soyuz’ meaning union. The association was founded in the summer of 2007 during the wedding ceremony of a colleague in London, the idea came about to form an umbrella organisation to bring together and embrace in friendship as it existed amongst us during our stay in the USSR was agreed.

Soyuznikis-UK is a secular and non political organisation. Membership to the group is not dependent on creed, origin, gender or sexuality. We endeavour to be a progressive organisation that will make meaningful contributions to the communities that gave us the opportunity to learn – USSR, the one that now host us - United Kingdom and most especially our nation – Nigeria. The deeds and acts of Soyuznikis-UK are guided by its constitution.

Our general meetings are held on the last Saturday of every month excluding December, when we normally hold our End of Year Party. Ideally, we as a group encourage our friends and familities to join us on our social events as a way of fostering our interpersonal relationships.

Unity Is Strength

Since inception, the association has been lead by the following persons as President. They have made efforts to foster growth and unity among members.

They are:
  1. Mr. Paul Eboh 2007 to 2009
  2. Dr. Ralph Eke 2009 to 2011
  3. Pastor Chioma Ejiofor 2011 to 2012
  4. Mr. Ebenezer Hundeyin 2012 to 2019
  5. Mr. Olushina Alaka 2019 to date


Cancel Culture - Very Divisive

The most dangerous of all falsehoods is slightly distorted truth. The danger of instant judgements and monolithic narratives are all too prevalent in these deliberations. Where you will find cold-blooded grasping; massive sense of entitlement; an inability to show gratitude; an unrealistic expectation of puritanism from others; and a passionate performance of virtue that is well executed in the public space ( social media) but not in the intimate space of co-habitation and friendship.

These are very trying times. Technology as recent as couple of years ago was supposed to bring us all closer - remember the global village?. The emergence of an old doctrine - critical race theory the epitome of this dramatic change in attitude towards anyone with a different point of view has put paid to that paradigm. These contrive and concerted attack on one race as being the source of the biblical original sin is trivial and false period.

We insulate ourselves in ideological bubbles of similar-thinking people and refuse to countenance or even engage with the truth. We now seems to be building echo chambers with titanium and carbon fibre cladding just to make sure we do not see or hear anything different. If these cancel culture mentality is being adopted to the pandemic, may be herd immunity would have been achieved by now. We have become communities in a dislocated social fabric that is fracturing at an astonishing rate. If we do not amend this fast, rupture seems to be the only ramification.